

In 1978, Chief Awolowo, the political leader of the Yoruba people in the 20th century, and our spiritual leader since then, wrote an anthem for the Yoruba people. His words cause hairs on the back of your neck to stand up and for you to beat your chest in pride.
Isẹ́ wà fún ilẹ̀ wa
Fún orilẹ ìbí wá
K'agbégá k'agbégá k'agbégá f'áyérí
Ìgbagbo wa ni wipé
b'áati b'ẹ́rú lab'ọ́mọ
Káṣiṣẹ́ káṣiṣẹ́ káṣiṣẹ́ kájọlà
Ìsọ̀kan àt'òmìnira
ni k'ẹ́ẹjẹ ká máa lépaa
'Tẹsiwáju ọ̀pọ̀ ire at'ohun tó dáraa
Ọmọ Odu'a dide
bọ́sí ipò ẹ̀tọ́ rẹ
Iwọ́ ní, imọ́lẹ́ gbogbo adúláwọ̀.
I have translated Awolowo’s words into English for the benefit of Yoruba people worldwide especially for the descendants of enslaved Yoruba people who now domicile in the Diaspora particularly in Brazil, Caribbean and Cuba. Yorubaland will forever be your Homeland.
Our responsibility to our Homeland
To the land of our birth
Is to lift it up, for the world to see
It is our belief
That we birth the slave same as we birth the child
That we work work work to liberate us all
Unity of purpose and freedom
Are what we should strive for
To advance in abundance and in what is good
The child of Oduduwa
Assume the position that befits you
For you are the light for all the dark skinned peoples